Tí ó bá sì jẹ́ pé wọ́n fa ẹ̀wù rẹ̀ ya lẹ́yìn, (obìnrin yìí) l’ó parọ́, (Yūsuf) sì wà nínú àwọn olódodo."
____________________
Ẹlẹ́rìí yìí ni ọmọ òpóǹló tí Allāhu (subhānahu wa ta'ālā) fún lọ́rọ̀ sọ lórí ìtẹ́. Nítorí náà, kì í ṣe ‘Īsā ọmọ Mọryam ('alaehi-ssọlātu wa-ssalām) nìkan ni ẹni tí ó sọ̀rọ̀ ní òpóǹló lórí ìtẹ́.


الصفحة التالية
Icon