Nítorí náà, ohùn igbe líle t’ó mi ilẹ̀ tìtì gbá wọn mú. Wọ́n sì di ẹni t’ó dà lulẹ̀, tí wọ́n ti dòkú sínú ìlú wọn.
Oríṣi ìyà méjì wọ̀nyí ni Allāhu (subhānahu wa ta'ālā) fi jẹ ìjọ Ànábì Ṣu‘aeb ('alaehi-ssọlātu wa-ssalām); ohùn igbe líle t’ó mi ilẹ̀ tìtì (sūrah Hūd; 11:94) àti ẹ̀ṣújò iná (sūrah aṣ-Ṣu‘arọ̄’; 26:189).
الترجمة اليورباوية